Jeremiah 5:14
14
Nítorí náà, báyìí ni
Olúwa
Ọlọ́run Alágbára wí:
“Nítorí tí àwọn ènìyàn ti sọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí;
Èmi yóò sọ ọ̀rọ̀ mi lẹ́nu wọn di iná,
àti àwọn ènìyàn wọ̀nyí di igi tí yóò jórun.
Copyright information for
YorBMYO